Header Include

الترجمة اليورباوية - أبو رحيمة ميكائيل

ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني.

QR Code https://quran.islamcontent.com/31/yoruba_mikail

قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلۡفَلَقِ

Sọ pé: “Mo sá di Olúwa òwúrọ̀ kùtùkùtù

Sọ pé: “Mo sá di Olúwa òwúrọ̀ kùtùkùtù

مِن شَرِّ مَا خَلَقَ

níbi aburú ohun tí Ó dá,[1]

[1] Allāhu ni Ẹlẹ́dàá gbogbo n̄ǹkan, ohun rere àti ohun burúkú.
níbi aburú ohun tí Ó dá,[1]

وَمِن شَرِّ غَاسِقٍ إِذَا وَقَبَ

àti níbi aburú òru nígbà tí ó bá ṣóòkùn,

àti níbi aburú òru nígbà tí ó bá ṣóòkùn,

وَمِن شَرِّ ٱلنَّفَّٰثَٰتِ فِي ٱلۡعُقَدِ

àti níbi aburú àwọn (òpìdán) tó ń fẹnu fátẹ́gùn túẹ́túẹ́ sínú àwọn ońdè,

àti níbi aburú àwọn (òpìdán) tó ń fẹnu fátẹ́gùn túẹ́túẹ́ sínú àwọn ońdè,

وَمِن شَرِّ حَاسِدٍ إِذَا حَسَدَ

àti níbi aburú onílara nígbà tí ó bá ṣe ìlara.”

àti níbi aburú onílara nígbà tí ó bá ṣe ìlara.”
Footer Include