الترجمة اليورباوية - أبو رحيمة ميكائيل
ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني.
قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلۡفَلَقِ
Sọ pé: “Mo sá di Olúwa òwúrọ̀ kùtùkùtù
Sọ pé: “Mo sá di Olúwa òwúrọ̀ kùtùkùtù
مِن شَرِّ مَا خَلَقَ
níbi aburú ohun tí Ó dá,[1]
[1] Allāhu ni Ẹlẹ́dàá gbogbo n̄ǹkan, ohun rere àti ohun burúkú.
níbi aburú ohun tí Ó dá,[1]
وَمِن شَرِّ غَاسِقٍ إِذَا وَقَبَ
àti níbi aburú òru nígbà tí ó bá ṣóòkùn,
àti níbi aburú òru nígbà tí ó bá ṣóòkùn,
وَمِن شَرِّ ٱلنَّفَّٰثَٰتِ فِي ٱلۡعُقَدِ
àti níbi aburú àwọn (òpìdán) tó ń fẹnu fátẹ́gùn túẹ́túẹ́ sínú àwọn ońdè,
àti níbi aburú àwọn (òpìdán) tó ń fẹnu fátẹ́gùn túẹ́túẹ́ sínú àwọn ońdè,
وَمِن شَرِّ حَاسِدٍ إِذَا حَسَدَ
àti níbi aburú onílara nígbà tí ó bá ṣe ìlara.”
àti níbi aburú onílara nígbà tí ó bá ṣe ìlara.”
مشاركة عبر