Header Include

الترجمة اليورباوية - أبو رحيمة ميكائيل

ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني.

QR Code https://quran.islamcontent.com/59/yoruba_mikail

قُلۡ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلنَّاسِ

Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,

Sọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,

مَلِكِ ٱلنَّاسِ

Ọba àwọn ènìyàn,

Ọba àwọn ènìyàn,

إِلَٰهِ ٱلنَّاسِ

Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]

[1] Ìtúmọ̀ “Ọlọ́hun àwọn ènìyàn” ni pé, Ẹni tí àwọn ènìyàn gbọ́dọ̀ máa jọ́sìn fún ní ọ̀nà òdodo, tí wọn kò sì gbọ́dọ̀ jọ́sìn fún ẹlòmíìràn lẹ́yìn Rẹ̀.
Ọlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]

مِن شَرِّ ٱلۡوَسۡوَاسِ ٱلۡخَنَّاسِ

níbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).

[1] Ọ̀kan pàtàkì nínú àǹfààní àti oore tí ó wà nínú ath-thikār ṣíṣe ni pé, aṣ-Ṣaetọ̄n àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ yóò máa sá sẹ́yìn fún ẹni tí ó bá ń ṣe ath-thikār ní gbogbo ìgbà.
níbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).

ٱلَّذِي يُوَسۡوِسُ فِي صُدُورِ ٱلنَّاسِ

(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.

(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.

مِنَ ٱلۡجِنَّةِ وَٱلنَّاسِ

(Ṣaetọ̄n náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”

(Ṣaetọ̄n náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”
Footer Include