الترجمة اليورباوية - أبو رحيمة ميكائيل
ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني.
أَرَءَيۡتَ ٱلَّذِي يُكَذِّبُ بِٱلدِّينِ
Sọ fún mi nípa ẹni tó ń pe Ọjọ́ Ẹ̀san ní irọ́!
Sọ fún mi nípa ẹni tó ń pe Ọjọ́ Ẹ̀san ní irọ́!
فَذَٰلِكَ ٱلَّذِي يَدُعُّ ٱلۡيَتِيمَ
Ìyẹn ni ẹni tó ń lé ọmọ-òrukàn dànù.
Ìyẹn ni ẹni tó ń lé ọmọ-òrukàn dànù.
وَلَا يَحُضُّ عَلَىٰ طَعَامِ ٱلۡمِسۡكِينِ
Kò sì níí gbìyànjú láti bọ́ mẹ̀kúnnù.
Kò sì níí gbìyànjú láti bọ́ mẹ̀kúnnù.
فَوَيۡلٞ لِّلۡمُصَلِّينَ
Ègbé ni fún àwọn (mùnááfìkí) tó ń kírun;[1]
[1] Pẹ̀lú ìrun wákàtí márààrún lójoojúmọ́ ní àsìkò rẹ̀, ó ti run gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wẹẹrẹ dànù. Ìrònúpìwàdà àti ìtọrọ-àforíjìn l’ó máa run àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ńláńlá dànù.
Ègbé ni fún àwọn (mùnááfìkí) tó ń kírun;[1]
ٱلَّذِينَ هُمۡ عَن صَلَاتِهِمۡ سَاهُونَ
àwọn tó ń gbàgbé láti kírun wọn ní àsìkò rẹ̀;
àwọn tó ń gbàgbé láti kírun wọn ní àsìkò rẹ̀;
ٱلَّذِينَ هُمۡ يُرَآءُونَ
àwọn tó ń ṣe ṣekárími;
àwọn tó ń ṣe ṣekárími;
وَيَمۡنَعُونَ ٱلۡمَاعُونَ
àti pé wọ́n ń hánnà ohun èlò (fún àwọn ènìyàn).
àti pé wọ́n ń hánnà ohun èlò (fún àwọn ènìyàn).
مشاركة عبر