الترجمة اليورباوية - أبو رحيمة ميكائيل
ترجمها الشيخ أبو رحيمة ميكائيل أيكوييني.
قُلۡ هُوَ ٱللَّهُ أَحَدٌ
Sọ pé: “Òun ni Allāhu, Ọ̀kan ṣoṣo.
Sọ pé: “Òun ni Allāhu, Ọ̀kan ṣoṣo.
ٱللَّهُ ٱلصَّمَدُ
Allāhu ni Aṣíwájú tí ẹ̀dá ní bùkátà sí níbi jíjọ́sìn fún Un àti títọrọ oore ní ọ̀dọ̀ Rẹ̀, tí Òun kò sì ní bùkátà sí wọn ní ọ̀nà kan kan.
Allāhu ni Aṣíwájú tí ẹ̀dá ní bùkátà sí níbi jíjọ́sìn fún Un àti títọrọ oore ní ọ̀dọ̀ Rẹ̀, tí Òun kò sì ní bùkátà sí wọn ní ọ̀nà kan kan.
لَمۡ يَلِدۡ وَلَمۡ يُولَدۡ
Kò bímọ. Wọn kò sì bí I.
Kò bímọ. Wọn kò sì bí I.
وَلَمۡ يَكُن لَّهُۥ كُفُوًا أَحَدُۢ
Kò sì sí ẹnì kan kan tí ó jọ Ọ́.”[1]
[1] Àwọn kan máa ń ké “Ƙul huwa-llāhu” mẹ́ta fún òkú mùsùlùmí. Nígbà mìíràn, wọ́n lè ké òdidi al-Ƙur’ān fún un. Ìwọ̀nyí kò tọ sunnah rárá. Sūrah al-Haṣr; 59:10 ti fún wa ní àdúà tó jẹmọ́ òkú àti alààyè.
Kò sì sí ẹnì kan kan tí ó jọ Ọ́.”[1]
مشاركة عبر