La traduction en yorouba - Aboû Raḥîmah Mickaël
Traduction des sens du Noble Coran
Traduit par Cheikh Aboû Raḥîmah Mickaël Aykwînî.
ٱلۡقَارِعَةُ
Àkókò ìjáyà.
مَا ٱلۡقَارِعَةُ
Kí ni Àkókò ìjáyà?
وَمَآ أَدۡرَىٰكَ مَا ٱلۡقَارِعَةُ
Kí sì l’ó mú ọ mọ ohun tó ń jẹ́ Àkókò ìjáyà?
يَوۡمَ يَكُونُ ٱلنَّاسُ كَٱلۡفَرَاشِ ٱلۡمَبۡثُوثِ
(Òhun ni) ọjọ́ tí ènìyàn yó dà bí àfòpiná tí wọ́n fọ́nká síta,
وَتَكُونُ ٱلۡجِبَالُ كَٱلۡعِهۡنِ ٱلۡمَنفُوشِ
àwọn àpáta yó sì dà bí ẹ̀gbọ̀n òwú tí wọ́n gbọ̀n dànù.
فَأَمَّا مَن ثَقُلَتۡ مَوَٰزِينُهُۥ
Nítorí náà, ní ti ẹni tí òṣùwọ̀n (iṣẹ́ rere) rẹ̀ bá tẹ̀wọ̀n,
فَهُوَ فِي عِيشَةٖ رَّاضِيَةٖ
ó sì máa wà nínú ìṣẹ̀mí tó máa yọ́nú sí.
وَأَمَّا مَنۡ خَفَّتۡ مَوَٰزِينُهُۥ
Ní ti ẹni tí òṣùwọ̀n (iṣẹ́ rere) rẹ̀ bá sì fúyẹ́,
فَأُمُّهُۥ هَاوِيَةٞ
Hāwiyah sì ni ibùgbé rẹ̀.
وَمَآ أَدۡرَىٰكَ مَا هِيَهۡ
Kí sì ni ó mú ọ mọ ohun tó ń jẹ́ bẹ́ẹ̀?
نَارٌ حَامِيَةُۢ
(Òhun ni) Iná gbígbóná tó ń jó gan-an.
share_via