La traduction en yorouba - Aboû Raḥîmah Mickaël
Traduction des sens du Noble Coran
Traduit par Cheikh Aboû Raḥîmah Mickaël Aykwînî.
إِنَّآ أَنزَلۡنَٰهُ فِي لَيۡلَةِ ٱلۡقَدۡرِ
Dájúdájú Àwa sọ al-Ƙur’ān kalẹ̀ nínú Òru Abiyì.[1]
[1] Ẹ wo ìtọsẹ̀-ọ̀rọ̀ sūrah al-’Isrọ̄’; 17:106.
Dájúdájú Àwa sọ al-Ƙur’ān kalẹ̀ nínú Òru Abiyì.[1]
وَمَآ أَدۡرَىٰكَ مَا لَيۡلَةُ ٱلۡقَدۡرِ
Kí sì ni ó mú ọ mọ ohun tó ń jẹ́ Òru Abiyì?
Kí sì ni ó mú ọ mọ ohun tó ń jẹ́ Òru Abiyì?
لَيۡلَةُ ٱلۡقَدۡرِ خَيۡرٞ مِّنۡ أَلۡفِ شَهۡرٖ
Òru Abiyì lóore ju ẹgbẹ̀rún oṣù.
Òru Abiyì lóore ju ẹgbẹ̀rún oṣù.
تَنَزَّلُ ٱلۡمَلَٰٓئِكَةُ وَٱلرُّوحُ فِيهَا بِإِذۡنِ رَبِّهِم مِّن كُلِّ أَمۡرٖ
Àwọn mọlāika àti Jibrīl yó sì máa sọ̀kalẹ̀ nínú òru náà pẹ̀lú àṣẹ Olúwa wọn fún gbogbo ọ̀rọ̀ ẹ̀dá kọ̀ọ̀kan.
Àwọn mọlāika àti Jibrīl yó sì máa sọ̀kalẹ̀ nínú òru náà pẹ̀lú àṣẹ Olúwa wọn fún gbogbo ọ̀rọ̀ ẹ̀dá kọ̀ọ̀kan.
سَلَٰمٌ هِيَ حَتَّىٰ مَطۡلَعِ ٱلۡفَجۡرِ
Àlàáfíà ni òru náà títí di àsìkò àfẹ̀mọ́júmọ́.
Àlàáfíà ni òru náà títí di àsìkò àfẹ̀mọ́júmọ́.
share_via